BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
01:36
Fídíò,
Àwọn ohun tí o lè ṣe rèé láti mú kí ọmọ rẹ má a jẹ èso àti ewébẹ̀ dáadáa
, Duration 1,36
02:21
Fídíò,
'Kò síná, kò sómi, àfi bí pé ìhòhò la wa ni, ọmọ ọdún méje kò fojú rínà ọba rí nílùú yìí'
, Duration 2,21
04:40
Fídíò,
Bí mo ṣe kọ́kọ́ rí àwòrán ọkọ mi lára àwọn tí wọ́n tú sílẹ̀ ní Ogbomoso mo ṣubú mo ń sun ẹkún ni - Ìyàwó ọ̀kan lára àwọn olùkọ́ tí wọ́n jí gbé
, Duration 4,40
01:20
Fídíò,
Yàtọ̀ sí oyún ìbejì,mọ̀ nípa bí obìnrin ṣe lè lóyún méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nínú kan ṣoṣo
, Duration 1,20
04:55
Fídíò,
Olùkọ́ tó ní ìpèníjà ojú kàwé gboyè Ọ̀mọ̀wé ní fásitì, ó ní ó wu òun láti jẹ́ amòfin, máa jà fún ọmọnìyàn
, Duration 4,55
04:20
Fídíò,
Oyún ọmọ mi kejì kò tíì pé oṣù mẹ́ta, tí mo fi kan ìdààmú nínú ìgbéyàwó, mo sun ṣégè ẹkún - Wasila Coded
, Duration 4,20
02:52
Fídíò,
"Ẹ má fi ìmọ̀ ẹ̀rọ ìtàkùn àgbàyé Tech wé Yahoo, èdé Yorùbá tí mo fí ń kọ́ ọ̀pọ̀ èèyàn ń mú kí owó wọlé fún wọn"
, Duration 2,52
01:23
Fídíò,
Ìdí tí wíwọ ṣòkòtò àwọ̀tẹ́lẹ̀ péńpé 'boxer' sún kò fi dára tó fún ọ
, Duration 1,23
05:31
Fídíò,
Ìbọn tí wọ́n yìn sí ọkọ mi kò ràn án, ìgbà tí wọ́n gba àpò ọwọ́ rẹ̀ ni ìbọn tó ràn án – ìyàwó ọmọ ẹgbẹ́ Accord tí wọ́n pa l'Esa Oke ṣalàyé
, Duration 5,31
04:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration 4,07
00:51
Fídíò,
Àǹfààní márùn-ún tó wà nínú kí obìnrin sùn láì wọ pátá
, Duration 0,51
03:45
Fídíò,
N kò le fẹ́ ọkùnrin tó lówó, n kò sì le bá ọkùnrin jìyà tàbí ṣe ìyàwó kejì àbí ìkẹta - Eyiyemi Afolayan
, Duration 3,45
05:08
Fídíò,
Emi ni obìńrin àkọ́kọ́ tí yóò lo wáyà iná tí kò wúlò láti ṣe iṣẹ́ ọ̀nà àwòrán - Patience Adekunle
, Duration 5,08
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ọkọ̀ bọ́ọ̀sì tó ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ ogún
wákàtí 2 sẹ́yìn
Ìjọba fojú mẹ́ta lára àwọn afurasí agbésùnmọ̀mí tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Ogbomoso hàn nílé ẹjọ́
wákàtí 4 sẹ́yìn
Ohun tí a mọ̀ nípa rògbòdìyàn tó wáyé l'Osogbo níbi tí èèyàn méjì ti kú, tí ọ̀pọ̀ tún farapa
wákàtí 6 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Wo ọ̀nà márùn-ún tí àwọn ọ̀dọ́ lè máa gbà rí owo gọbọi
13 Agẹmo 2026
Alága àdúgbò dá baálé ilé dọ́bálẹ̀, fi pankẹ́rẹ́ dá sẹ̀ríà ìyà fún un torí pé ó sọ̀rọ̀ lórí àṣepatì àkànṣeiṣẹ́ àjọ NDDC, ọlọ́pàá ní iléẹjọ́ yá
13 Agẹmo 2026
Ọdún méjìdínlógún ni mo fi wojú Ọlọ́run fọ́mọ kí n tó bí ìbejì - Ricardo Agbor
11 Agẹmo 2026
Ìjọba Nàíjíríà ṣe àfikún lórí owó oṣù àwọn ọmọ ogun láti 49,000 sí 100,000 náírà
11 Agẹmo 2026
"Àkọ̀bí mi tó ń tọ́jú èmi àtàwọn àbúrò rẹ̀ ní wọ́n pa nínú ìjà Hausa àti Yorùbá n'Ibadan"
10 Agẹmo 2026
Àlàyé lóríi bí àjọ NDLEA ṣe mú afurasí ọmọ South Africa kan l'Abuja lórí ẹ̀sùn pé ó gbé oògùn olóró Heroin
12 Agẹmo 2026
Sunday Igboho sọ ìdí tí ìjọba ṣe kọ̀ láti sanwó ìtúsílẹ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
12 Agẹmo 2026
Iléẹṣẹ́ ológun Nàìjíríà ṣàlàyé iṣẹ́ oṣù kan tí wọ́n fi gba akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ Oríire lọ́wọ́ ajínigbé
12 Agẹmo 2026
Èyí ni àpéjọpọ̀ ẹ̀sìn márùn-ún táwọn èèyàn ti máa ń pọ̀jù lágbàáyé
12 Agẹmo 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ohun tí a mọ̀ nípa rògbòdìyàn tó wáyé l'Osogbo níbi tí èèyàn méjì ti kú, tí ọ̀pọ̀ tún farapa
2
Ìjọba fojú mẹ́ta lára àwọn afurasí agbésùnmọ̀mí tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Ogbomoso hàn nílé ẹjọ́
3
Aisha Achimugu, bọ̀rọ̀kìnní obìnrin tí iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀lé ẹ̀ṣọ́ ara àti ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí owó rẹ̀ tó ₦8.9bn lẹ́yìn tí EFCC fí ẹ̀sùn kíkọ́rọ̀ jọ lọ́nà èrú kàn án
4
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ọkọ̀ bọ́ọ̀sì tó ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ ogún
5
Wo bí 'Muhammad' ṣe di orúkọ tí wọ́n ń sọ ọmọkùnrin jùlọ ní England àti Wales
6
Ìjọba, ẹ bá wa ṣètò láti gbé òkú ọkọ mi wálé ká lè sin ín, ẹ sì ràn mí lọ́wọ́ lórí ètò ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ - Ìyàwó John Olaleye
7
Gbogbo ìgbà ti ọmọ mi bá rí àlejò ni ẹ̀rù máa ń bà á báyìí – Ìyá akẹ́kọ̀ọ́ tó gba ìtúsílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo
8
Wo àwọn orílẹ́-èdè ilẹ̀ Afirika táwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kò gbọdọ̀ lọ
9
Òjò yóò rọ̀ fún ọjọ́ mẹ́wàá gbáko – Àyẹ̀wò ojú ọjọ́
10
Ilé aṣòfin Amẹrika buwọ́lù àbá láti dá ìrànwọ́ Amẹrika fún Naijiria dúró títí tíjọba yóò fi wá ojútùú sí ìṣekúpani àwọn Kristẹni