BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipese Aabo fun ilu
Ọmọdé méjì kú lásìkò tí ọ̀dọ́kùnrin kan yìnbọn nílé ẹ̀kọ́ Ìjọ Kátólìíkì
28 Ògún 2025
4:33
Fídíò,
'Mi ò ní ₦30 lọ́wọ́ àmọ́ ajínigbé ní kí n mú 30m wáà fi gba ọmọ mi méjì tí wọ́n gbé'
, Duration 4,33
25 Ògún 2025
Ọ̀dọ́bínrin Bidemi kú sílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ Yinka l'Osun, Yinka dèrò àhámọ́, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
25 Ògún 2025
Sunday Igboho fi ìdọ̀bálẹ̀ tọ̀rọ àforíjìn lọ́wọ́ Ooni, ó rí ìdáríjì gbà
24 Ògún 2025
"Àwọn Fijilanté tó já mi sí ìhòòhò, halẹ̀ mọ́ mi pé àwọn yóò yìnbọn pa mi, ju òkú mi sínú igbó"
23 Ògún 2025
Aráàlú lu obìnrin tó ń rìn gbéregbère kiri pa, wọn ló jọ ajínigbé
23 Ògún 2025
Ìdí tí ilé ẹjọ́ fi gbẹ́sẹ̀ lé àkáǹtì owó mẹ́rin tó jẹ́ ti Mele Kyari, ọ̀gá àgbà tẹ́lẹ̀ fájọ NNPCL
22 Ògún 2025
Àwọn afurasí agbésùnmọ̀mí tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì ìlú Owo ní ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Al-Shaba – DSS
21 Ògún 2025
Adigunjalè kọlu Lil Kesh, akọrin takasúfèé, wọ́n gún un lọ́bẹ lọ́rùn, gba ẹ̀ṣọ́ ara olówó iyebíye lọ́wọ́ rẹ̀
21 Ògún 2025
Makinde ṣàbẹ̀wò sí Fresh FM iléeṣẹ́ rédíò Ayefele tó jóná, ó ṣèlérí ìrànwọ́
17 Ògún 2025
Ọwọ̀ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin kan pẹ̀lu N25 million tó fẹ́ẹ́ pín níbi ìdìbò
16 Ògún 2025
1:34
Fídíò,
'Ìlú tó léwu láti gbé jùlọ fún àwọn obìnrin lágbáyé'
, Duration 1,34
16 Ògún 2025
Ìjọba sàlàyé ìdí abájọ ipò 'àmbásádọ̀' nípa ọ̀rọ̀ ìrìnnà òfúrufú tó fún KWAM 1, ọ̀pọ̀ èèyàn fọnmú
14 Ògún 2025
Ìdí tí ìjọba fi fagilé ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kan Kwam 1, mú àdínkù bá ìjìyà rẹ̀
13 Ògún 2025
Wo bí ẹlẹ́wọ̀n 16 ṣe ṣá kúrò lọ́gbà ẹ̀wọ̀n ní Nasarawa,
13 Ògún 2025
Àwọn aráàlú Babanla, ní Kwara ti ń fi ìlú sílẹ̀ lẹ́yìn ìkọlù agbébọn
12 Ògún 2025
A kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ìkọlù ṣọ́ọ̀ṣì Kátólíkì, St. Francis ìlú Owo – Àwọn afurasí sọ fún adájọ́
11 Ògún 2025
Sowore gba ìtúsílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ méjì ní àtìmọ́lé ọlọ́pàá
9 Ògún 2025
Àlàyé rèé lórí ìlú kan ní Kwara tí wọ́n ló di ahoro nítorí ìkọlu àwọn agbébọn
7 Ògún 2025
5:34
Fídíò,
'Àsìkò tó yẹ kí n máa jèrè wàhálà mi lórí ọmọ mi ni wọ́n pá níbi iṣẹ́'
, Duration 5,34
4 Ògún 2025
Obìnrin tó kun Nọ́ọ̀sì olóyún wẹ́lẹwẹ̀lẹ, tó tún ń ta ẹ̀yà ara èèyàn fáwọn Babaláwo, wọ gàù ọlọ́pàá
1 Ògún 2025
Lawal Adefalu, bàbá Hasfot Yetunde sọ̀rọ̀, nípa ìdájọ́ lórí ikú ọmọ rẹ̀
1 Ògún 2025
"Èròjà òògùn owó tó lé gbé N4m wá lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, tí wọn rí nínú ilé Abdulrahman fihàn pé ó múra sílẹ̀ láti fi Yetunde ṣe òògùn owó ni"
31 Agẹmo 2025
Ẹ̀gbọ́n gé orí abúrò rẹ̀ l‘Ondo, aráàlú dá àjọ ìyà fun, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ
30 Agẹmo 2025
Ìṣájú
Page
15
nínú
40
1
12
13
14
15
16
17
18
40
Tókàn