BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipese Aabo fun ilu
Akẹ́kọ̀ọ́ mọ̀kànlá nínú 303 tilé ẹ̀kọ́ St Mary Catholic ní Niger bọ́ lọ́wọ́ agbebọn, bí Gómìnà Kebbi ṣe fẹ́ fa akẹ́kọ̀ọ́ 24 tó dé láti ọ̀dọ̀ ajínigbé, lé òbí wọn lọ́wọ́
26 Bélú 2025
Àwọn afurasí Adanranjẹ̀ ló ya wọ Isapa, yìnbọn lu ìyá àgbà, a ti wọnú igbó lọ pẹ̀lú Fijilańté láti gba èèyàn mẹ́wàá tí wọn jí gbé padà - Ọlọ́pàá Kwara
26 Bélú 2025
Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tíwà ìjínigbé tí gogò ní Nàíjíríà, kí ló dé tí ìjọba kò ṣe tí ì rẹ́yìn rẹ̀?
25 Bélú 2025
Olúgbohùn ni wọ́n fi bá ìyàwó mi sọ̀rọ̀, wọ́n ti ra á níyè kó tó tẹ̀lé wọn, kìí ṣe ojú lásán - Ọkọ òṣìsẹ́ FRSC tí wọn pa òun àti ọmọ rẹ̀ ṣàlàyé
25 Bélú 2025
Orílẹ́èdè Afirika mẹ́wàá tí ìjọba ti náwó jùlọ lórí ètò ààbò lọ́dún 2025
22 Bélú 2025
Ọlọ́pàá Kwara bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ikú obìnrin tí wọ́n fún lọ́rùn pa nílé ìtura kan ní Ilorin
22 Bélú 2025
Agbébọn ṣe ìkọlù tuntun ní Kwara, ṣekúpa èèyàn méjì, jí mẹ́rin gbé lọ
20 Bélú 2025
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara gbé àwọn ilé ẹ̀kọ́ tì pa níjọba ìbílẹ̀ márùn-ún torí ètò ààbò tó mẹ́hẹ
20 Bélú 2025
Àwọn ọ̀dọ́ ìlú Eruku fẹ̀hónú hàn, nítorí ìpànìyàn tó wáyé ní ṣọ́ọ̀ṣì CAC ní Kwara
19 Bélú 2025
Irọ́ ni pé àwọn kan fẹ́ gbẹ̀mí Yerima nílùú Abuja – Ọlọ́pàá
17 Bélú 2025
Ní ọjọ́ tí mo gba ọ̀pá àṣẹ Ọba ìlú Eko, ni mo ṣàdúrà pé kí Tinubu di ààrẹ Nàìjíríà - Ọba Akiolu
11 Bélú 2025
Kókó tó wà nínú èsì Tinubu sọ́rọ̀ tí Trump sọ nípa Naijiria lórí ẹ̀sùn ìṣekúpani àwọn Kristẹni
7 Bélú 2025
Àwọn ọ̀dọ́ lu Ìmáàmù àgbà kan pa ní Kwara; Ohun tí a mọ̀ nípa rẹ̀ rèé
6 Bélú 2025
Wo ìdí tí iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS fi yọ òṣìṣẹ́ 115 bí ẹní yọ jìgá
5 Bélú 2025
Ìyàwó mi di àwátì nílùú Abuja, kò lè sọ̀rọ̀ mọ́ nígbà tí mo padà rí i nípìńlẹ̀ Sokoto
3 Bélú 2025
Wo àwọn ìpínlẹ̀ tí aráàlú ti fẹ̀sùn aṣemáṣe lẹ́nu iṣẹ́ kan ọlọ́pàá jùlọ ní Naijiria
3 Bélú 2025
Àwọn agbébọn jí Igbákejì olórí ilé ìgbìmọ̀ aṣofin Kebbi gbé
1 Bélú 2025
Ọlọ́pàá àti èèyàn kan fara gbọta báwọn adigunjalè ṣe kọlu ọkùnrin kan tó lọ gbá owó ní Báńkì n‘Ibadan
28 Ọ̀wàrà 2025
3:47
Fídíò,
"Mo ní ìjàmbá ọkọ̀ lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá, n kò le rìn mọ́, mo ná N25m ẹ̀yáwó báńkì lórí àárẹ̀, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kò yà sí mi, ìran mi kò lè ṣe iṣẹ́ ọlọ́pàá mọ́"
, Duration 3,47
28 Ọ̀wàrà 2025
"Obìnrin díjà sílẹ̀ láàárín ọ̀rẹ́ méjì, Gafaru àti Tunde n'Ilorin, ni Gafaru bá bínú gún Tunde pa"
25 Ọ̀wàrà 2025
Kí ló dé tí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá nawọ́ gan Omoyele Sowore lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ gba bẹ́ẹ̀lì rẹ̀ pẹ̀lú àbúrò Nnamdi Kanu?
24 Ọ̀wàrà 2025
Ààrẹ Tinubu pààrọ̀ àwọn olórí ẹ̀ṣọ́ aláàbò, kéde àwọn tuntun
24 Ọ̀wàrà 2025
Kí ni ìdí tí Sultan Sokoto ṣe ń pè fún fífọwọ́ tó le mú àṣìlò ojú òpó ayélujára ní Nàìjíríà?
22 Ọ̀wàrà 2025
Ṣé lóòòtọ́ọ́ ni ìjìyà wà fún ẹnikẹ́ni tó bá fún obìnrin lóyún láì ṣètọ́jú rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Eko? Ohun tí a mọ̀ rèé
21 Ọ̀wàrà 2025
Ìṣájú
Page
12
nínú
40
1
9
10
11
12
13
14
15
40
Tókàn