BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipese Aabo fun ilu
Ìjọba fojú mẹ́ta lára àwọn afurasí agbésùnmọ̀mí tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Ogbomoso hàn nílé ẹjọ́
17 Agẹmo 2026
Ohun tí a mọ̀ nípa rògbòdìyàn tó wáyé l'Osogbo níbi tí èèyàn méjì ti kú, tí ọ̀pọ̀ tún farapa
17 Agẹmo 2026
Gbogbo ìgbà ti ọmọ mi bá rí àlejò ni ẹ̀rù máa ń bà á báyìí – Ìyá akẹ́kọ̀ọ́ tó gba ìtúsílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo
17 Agẹmo 2026
Ìjọba, ẹ bá wa ṣètò láti gbé òkú ọkọ mi wálé ká lè sin ín, ẹ sì ràn mí lọ́wọ́ lórí ètò ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ - Ìyàwó John Olaleye
17 Agẹmo 2026
Baálé ilé lu ìyàwó rẹ̀ pa nítorí oúnjẹ, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
16 Agẹmo 2026
''Ohun tó kàn fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oríire tó bọ́ lọ́wọ́ ajínigbé rèé, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ọ́...''
16 Agẹmo 2026
Èyí lohun tí MC Oluomo, Sego sọ̀rọ̀ lórí ikú tó pa Toba Ijaya, akọ̀wé NURTW ní ìpínlẹ̀ Eko
15 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá mú afurasí ajọ́mọgbé méjì n'Ibadan, dóòlà ọmọ ọdùn márùn-un tí wọ́n jí gbé
15 Agẹmo 2026
''Makinde ní láti tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé, àjọ UNO tó ń ké pè kò lè sèwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà''
15 Agẹmo 2026
Àwọn agbófinró nawọ́ gán Adeyemi, Ọ̀gá àgbà ayédèrú àjọ PFIPC lẹ́yìn tó kọ̀ láti yọjú sílé ẹjọ́
14 Agẹmo 2026
Alága àdúgbò dá baálé ilé dọ́bálẹ̀, fi pankẹ́rẹ́ dá sẹ̀ríà ìyà fún un torí pé ó sọ̀rọ̀ lórí àṣepatì àkànṣeiṣẹ́ àjọ NDDC, ọlọ́pàá ní iléẹjọ́ yá
13 Agẹmo 2026
Àlàyé lóríi bí àjọ NDLEA ṣe mú afurasí ọmọ South Africa kan l'Abuja lórí ẹ̀sùn pé ó gbé oògùn olóró Heroin
12 Agẹmo 2026
Àwọn ajínigbé de àwọn olùkọ́ ọkùnrin tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso mọ́lẹ̀, wón tún fi aṣọ bò wọ́n lójú fún ọjọ́ mérìndínlọ́gọ́ta - Soun
11 Agẹmo 2026
Àwọn afurasí tò ṣekúpa òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì OGTV fojú ba ilé ẹjọ́, bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ rèé
9 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo gbẹ̀mí afurasí ajínigbé méjì lójú ọ́nà Owo lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìbọn fúnra wọn
9 Agẹmo 2026
Agbèsùnmọ̀mí pa ṣọ́já, dàná sun àgọ́ ọlọ́pàá, iléèwòsàn àti yàrá ìkàwé
9 Agẹmo 2026
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
8 Agẹmo 2026
"Abuja ni ọmọ mi ní òun ti ń ṣiṣẹ́, kìí ṣe oníjọ̀ngbọ̀n, àhésọ̀ ọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ kò yé mi tí ọlọ́pàá ṣe ba irin ara ògiri àti ìlẹ̀kùn ilé jẹ́ láti fi tipá wọlé"
8 Agẹmo 2026
Ọmọ Naijiria méjì kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá àti lásìkò ìkọlù ní South Africa, ìjọba àpapọ̀ fọnmú, bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
8 Agẹmo 2026
Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà
7 Agẹmo 2026
Ọmọ ọdún méjìlélógún ṣàlàyé bó ṣe jí ara rẹ̀ gbé, tó sì ń bèèrè N25m owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí rẹ̀
6 Agẹmo 2026
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
6 Agẹmo 2026
"N25.5m, àpò ìrẹsì, epo pẹtiró àtàwọn nńkan míì ni ajínigbé gbà lọ́wọ́ wa, káwọn èèyàn wa ní Eda Oniyo tó gba ìtúsílẹ̀, Irọ́ ni, àwa ọlọ́pàá, ológun, Àmọ̀tẹ́kùn ló gbà wọ́n sílẹ̀"
6 Agẹmo 2026
Olórí ọmogun Naijiria ṣàlàyé ibi tí iṣẹ́ dé lori ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
5 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn