BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ehonu
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ yarí pé òun yóò gùnlé ìyanṣẹ́lódí, bí Hamas ṣe ju okú ọmọ Israel mẹ́fà tó wà ní àhámọ́ síta
2 Owewe 2024
Àwọn ọmọ ilẹ̀ òkèèrè tò dèrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn gbígbé àsìá Russia sókè ní Kano ti gbòmìnira
28 Ògún 2024
Ọlọ́pàá pa lára àwọn ọmọ ìjọ wa nílùú Abuja - Shiites
26 Ògún 2024
Olùwọ́de #EndSARS mẹ́fà gba ìtúsílẹ̀ lẹ́yìn ọdún mẹ́rin ní àtìmọ́lé
23 Ògún 2024
Ó lé ní èèyàn 1,000 tó wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn ìwọ́de ìlú le – Amnesty International
17 Ògún 2024
Àwọn obìnrin ṣe ìwọ́de alẹ̀ torí dókítà obìnrin tí wọn pa lẹ́yìn tí wọn fipá bá a lòpọ̀ nílé ìwòsàn
15 Ògún 2024
Àwọn olùwọ́de ebi ń pa mí, tó yabo ilé ẹjọ́ giga ní Kano, ti jí fáìlì ẹjọ́ ìwà àjẹbanu Ganduje lọ - Ìjọba
15 Ògún 2024
Buhari, Jonathan, Gowon, Abubakar péjú síbi ìpàdé ìgbìmọ̀ Májẹ̀óbàjẹ́, ṣe káre sí Tinubu pé kò gbà fáwọn olùwọ́de láti dojú ìjọba rẹ̀ bolẹ̀
14 Ògún 2024
Òní ni àṣekágba ìwọ́de ‘ebi ń pa wá’ #EndBadGovernance, àwọn nǹkan tó ṣẹlẹ̀ láàrin ọjọ́ mẹ́wàá rèé
10 Ògún 2024
Àwọn mọ̀lẹ́bí ọkùnri tí ọlọ́pàá ṣekúpa lásìkò ìwọ́de ìlú le bèrè ìdájọ́ òdodo
10 Ògún 2024
A kò mọ ohunkóhun nípa ìkọlù sí olú iléeṣẹ́ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC l'Abuja - Àjọ DSS
9 Ògún 2024
Owó tí iye rẹ̀ tó ₦3b ni a pàdánù lásìkò tí ìjọba kéde òfin kónílé-ó-gbélé – Àwọn oníṣòwò ẹkùn àríwá Nàìjíríà
8 Ògún 2024
Èmi ni mo pe ọmọ mi kó jáde wá fẹ̀hónúhàn tí ó fi ṣàgbákò ikú òjijì - Ìyá ọmọkùnrin tó kú
7 Ògún 2024
Ìjìyà tó wà lábẹ́ òfin fáwọn èèyàn tó ń gbé àsìá Russia sókè ní Nàìjíríà rèé
7 Ògún 2024
''Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti máwọn ọmọ ilẹ̀ òkèèrè tó ń ṣàtìlẹyìn fáwọn tó ń na àsìá Russia sókè níbí ìwọ́de''
7 Ògún 2024
Wo bí àwọn èèyàn Bangladesh ti ṣe ìwọ́dé tí Olóòtù ìjọba orílẹ́èdè náà sì kọ̀wé fipò sílẹ̀ sálọ
6 Ògún 2024
Èyin ọmọ Nàìjíríà tí ẹ fẹ́ lọ sí UK lásìkò yìí ẹ ṣọ́ra o torí rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀, ìjọba Tinubu kìlọ̀
6 Ògún 2024
Wo ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna fi tẹ̀lé ìgbésẹ̀ Kano, Yobe àtàwọn ìpínlẹ̀ míràn láti kéde kónílé-ó-gbélé
5 Ògún 2024
Wo àwọn kókó tí arààlú ń fẹ́ kí Tinubu mẹ́nubà ṣùgbọ́n tí Aàrẹ kò sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀
5 Ògún 2024
1:35
Fídíò,
Arábìnrin tó gbé ìkòkò tí kò sí nǹkan nínú rẹ̀ lọ síbi ìwọ́de l'Eko ṣàlàyé ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀
, Duration 1,35
5 Ògún 2024
Kò rọrùn láti yọ owó ìrànwọ́ epo bẹntiró àmọ́ ohun tó ṣe pàtàkì ni – Tinubu
4 Ògún 2024
Ewu tó wà lára afẹ́fẹ́ tajútajú 'Tear gas' àti iṣẹ́ tó ń ṣe lára èèyàn?
3 Ògún 2024
Wo ohun tí Tinubu àti àwọn gómìnà sọ lórí ìwọde #EndBadGovernance tó wáyé
3 Ògún 2024
Wo àwọn ìròyin òfégè tó ń jáde nípa ìwọ́de #EndBadGovernment tó ń lọ lọ́wọ́ ní Naijria
3 Ògún 2024
Ìṣájú
Page
6
nínú
28
1
2
3
4
5
6
7
8
9
28
Tókàn