BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipinlẹ Oyo
Kò ṣée má gbọ̀ọ́
25 Ẹrẹ̀nà 2025
Ẹ̀yin awakùsà lọ́nà àìtọ́, agbégbọn, ajínigbé, ẹ dẹ́kun ìwà àìda, bíbẹ́ẹ̀kọ́, máà ba ojú yín jẹ́ - Makinde kìlọ̀
21 Ẹrẹ̀nà 2025
Irọ́ ni ìjọba Oyo pa lórí oyè Eleruwa, agbára atóbi má ṣeé báwí ni ó lò lé wa lórí - Ìdílé Laribikusi fapá jánú
20 Ẹrẹ̀nà 2025
Aláàfin Owoade kéde kókó ohun tí yóò ṣe lórí ìtẹ́
18 Ẹrẹ̀nà 2025
Kehinde Subair, ọmọ ilé ìgbìmọ̀-aṣòfin Oyo tẹ́lẹ̀ jáde láyé
14 Ẹrẹ̀nà 2025
8:16
Fídíò,
Bí ilé ẹjọ́ ṣe kọ́kọ́ yọ mi nípò Eleruwa, jẹ́ kí n gbóòrùn ara mi - Eleruwa
, Duration 8,16
10 Ẹrẹ̀nà 2025
Aláàfin Oyo, Ọba AbdulAkeem Owoade bẹ̀rẹ̀ orò ìpèbí lẹ́yìn oṣù kan tó gba ọ̀pá àṣẹ
8 Ẹrẹ̀nà 2025
Ìdí rèé tí ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ fi lé Eleruwa, Ọba Adebayo Adegbola kúrò lórí ìtẹ́, kí Makinde tó yàn-án padà lẹ́yìn ọdún mẹ́fà
7 Ẹrẹ̀nà 2025
Eleruwa tuntun gba ọ̀pá àṣẹ, ìwé ẹ̀rí
6 Ẹrẹ̀nà 2025
Ta ló ń ro ikú ro Olubadan tí ariwo ikú rẹ̀ fi gbalẹ̀ kan?
4 Ẹrẹ̀nà 2025
''Mo fi ara mi sílẹ̀ fáwọn ajínigbé nígbà tí wọ́n fẹ́ máa mú ìyàwó mi lọ''
3 Ẹrẹ̀nà 2025
Ansoogun ògbóǹtarìgì jagunjagun Iresa Adu l'Ogbomoso 'tó bínú di òkúta pẹ̀lú àwọn ẹrú rẹ̀'
2 Ẹrẹ̀nà 2025
Ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn gbé ìdájọ́ kalẹ̀ lórí ìyànsípò Ọba Ghandi Olaoye gẹ́gẹ́ bíi Soun Ogbomoso
18 Èrèlè 2025
Akẹ́kọ̀ọ́ Poly Ibadan mẹ́wàá dèrò iléèwòsàn lẹ́yìn tí wọ́n fa gáàsì olóró símú
12 Èrèlè 2025
Adelabu ṣèpàdé pẹ̀lú IBEDC lórí ìdákúrekú iná mọ̀nàmọ́ná ní UCH
10 Èrèlè 2025
4:34
Fídíò,
Ní ìlú Igbeti òkúta iyebíye Marble ya mùrá síbẹ̀, àmọ́ kò so èso sí àpò aráàlú
, Duration 4,34
6 Èrèlè 2025
Ilé aṣòfin Oyo ní kí àwọn tó tàbùkù Soun Ogbomoso lórí rédíò Lagelu FM wá sọ tẹnu wọn
6 Èrèlè 2025
Lórí ọ̀rọ̀ ikú Bola Ige, Bisi Akande, Rashidi Ladoja sọ òkò ọ̀rọ̀ sí ara wọn
4 Èrèlè 2025
MURIC ní Shariah ti bẹ̀rẹ̀ n'Ibadan, Eko àti Abeokuta, àjọ CAN, Afenifere àtàwọn oníṣẹ̀ṣe fèsì sọ́rọ̀ Sultan
31 Sẹ́rẹ́ 2025
Ètò ìsìnkú Moses Korede, tí ọ̀pọ̀ mọ sì Bàbá Gbenro, tí bẹrẹ nilu Ogbomoso
31 Sẹ́rẹ́ 2025
Ìdí rèé tí Makinde fi ní káwọn òṣìṣẹ́ Oyo máa wọ Aṣọ Òkè ní gbogbo Ọjọ́bọ
30 Sẹ́rẹ́ 2025
Oriyomi Hamzat padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Agodi pẹ̀lú ọ̀pọ̀ ẹ̀bún lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjí tó kúrò níbẹ̀
29 Sẹ́rẹ́ 2025
Àwọn tó ń wa kùsà láìtọ́ ló ń kó Boko Haram àti ISWAP wọ ilẹ̀ Yorùbá - Gani Adams
28 Sẹ́rẹ́ 2025
Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde pàdánù ẹ̀gbọ́n rẹ̀
24 Sẹ́rẹ́ 2025
Ìṣájú
Page
12
nínú
40
1
9
10
11
12
13
14
15
40
Tókàn